Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ṣé Wàá Fẹ́ Ká Bẹ̀ Ọ́ Wò?

Ṣé Wàá Fẹ́ Ká Bẹ̀ Ọ́ Wò?

Ṣé Wàá Fẹ́ Ká Bẹ̀ Ọ́ Wò?

Àní nínú ayé onídààmú yìí, ìmọ̀ pípéye látinú Bíbélì nípa Ọlọ́run, Ìjọba rẹ̀, àti ohun àgbàyanu tó fẹ́ ṣe fún aráyé lè fún ọ láyọ̀. Bó o bá fẹ́ ìsọfúnni síwájú sí i tàbí tó o fẹ́ kí ẹnì kan kàn sí ọ nílé láti kọ́ ẹ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì lọ́fẹ̀ẹ́, jọ̀wọ́ kọ̀wé sí Jehovah’s Witnesses, P.M.B. 1090, Benin City 300001, Edo State, Nigeria, tàbí sí àdírẹ́sì tó bá yẹ lára èyí tí a tò sí ojú ìwé 2.