Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Ìrírí Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà

Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń gbìyànjú láti fi Bíbélì, Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run darí ohun tí wọ́n ń rò, ọ̀rọ̀ wọn àti ìṣe wọn. Wo ìyípadà tó mú kó ṣẹlẹ̀ nínú ayé wọn àtàwọn tó wà láyìíká wọn.

ÌRÍRÍ

Àlùfáà Kan Rí Ìdáhùn sí Ìbéèrè Rẹ̀

Lẹ́yìn tọ́mọ wọn kú, àlùfáà kan àti ìyàwó rẹ̀ sunkún gan-an. Kò pẹ́ sígbà yẹn ni wọ́n rí ìdáhùn tó tẹ́ wọn lọ́rùn sí àwọn ìbéèrè wọn nípa ikú.

ÌRÍRÍ

Àlùfáà Kan Rí Ìdáhùn sí Ìbéèrè Rẹ̀

Lẹ́yìn tọ́mọ wọn kú, àlùfáà kan àti ìyàwó rẹ̀ sunkún gan-an. Kò pẹ́ sígbà yẹn ni wọ́n rí ìdáhùn tó tẹ́ wọn lọ́rùn sí àwọn ìbéèrè wọn nípa ikú.

Bíbélì Máa Ń Yí Ìgbésí Ayé Àwọn Èèyàn Pa Dà