Ìròyìn
ÌRÒYÌN
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #7
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa àwọn nǹkan amóríyá tó ṣẹlẹ̀ ní Ọdún Iṣẹ́ Ìsìn 2025 àti bí Jèhófà ṣe bù kún iṣẹ́ tá a ṣe kárí ayé.
ÌRÒYÌN
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #7
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa àwọn nǹkan amóríyá tó ṣẹlẹ̀ ní Ọdún Iṣẹ́ Ìsìn 2025 àti bí Jèhófà ṣe bù kún iṣẹ́ tá a ṣe kárí ayé.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #5
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa àwọn ìlànà Bíbélì tó máa ràn wá lọ́wọ́ láti ṣèpinnu tó bọ́gbọ́n mu lórí ọ̀rọ̀ àfikún ẹ̀kọ́.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #4
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa àwọn ìlànà Bíbélì tó máa ràn wá lọ́wọ́ ká lè ṣe ìpinnu tó bọ́gbọ́n mu tó bá dọ̀rọ̀ àwọn àṣà ìbílẹ̀ kan àti lílo àwọn àmì tàbí àwòrán kan.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #3
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa ohun tá a lè ṣe tó máa jẹ́ ká lè ṣe púpọ̀ sí i lẹ́nu iṣẹ́ ìsìn Jèhófà láwọn oṣù tó ń bọ̀.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #2
Nínú ìròyìn yìí, a sọ̀rọ̀ nípa àwọn nǹkan tá à ń ṣe ká lè kọ́ àwọn ará kí wọ́n lè kàwé dáadáa, àti bí ẹbọ ìràpadà Jésù ṣe mú kí ọkàn wa balẹ̀. A tún sọ̀rọ̀ nípa orin tuntun tá a máa kọ ní àpéjọ agbègbè tọdún 2025.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2025 #1
Nínú ìròyìn yìí, a máa rí bá a ṣe lè lo apá “Ohun Tá À Ń Kọ́ Àwọn Èèyàn” tó wà ní àfikún A nínú ìwé Nífẹ̀ẹ́ Àwọn Èèyàn—Máa Sọ Wọ́n Dọmọ Ẹ̀yìn. Apá yìí máa jẹ́ ká lè bá àwọn èèyàn sọ̀rọ̀ lóde ìwàásù, ká sì gbádùn ẹ̀.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #8
Nínú ìròyìn yìí, àá sọ̀rọ̀ nípa bó ṣe yẹ ká máa ṣe sí àwọn tó bá kópa nínú àwọn fídíò wa.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #7
Nínú ìròyìn yìí, a máa gbọ́ nípa bí nǹkan ṣe ń lọ fáwọn ará wa kárí ayé, àá sì gbọ́rọ̀ lẹ́nu Arákùnrin Jody Jedele àti Arákùnrin Jacob Rumph tó ṣẹ̀ṣẹ̀ di ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #6
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa ìdí tí kò fi yẹ ká ṣíwọ́ àtimáa bẹ̀rẹ̀ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #5
Nínú ìròyìn yìí, a máa rí ohun tá a lè ṣe táá mú ká túbọ̀ fọkàn sí i pé Ìjọba Ọlọ́run nìkan ṣoṣo ló lè yanjú ìṣòro aráyé.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #4
Nínú ìròyìn yìí, a máa rí báwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́ ṣe ń “fi ire ṣẹ́gun ibi.”—Róòmù 12:21.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #3
Nínú ìròyìn yìí, a máa jíròrò àwọn ìlànà Bíbélì tó máa jẹ́ ká lè ṣèpinnu tó dáa tó bá dọ̀rọ̀ ìmúra wa.
Ìròyìn Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí ti Ọdún 2024 #2
Nínú ìròyìn yìí, a máa sọ̀rọ̀ nípa bí Jèhófà Baba wa onífẹ̀ẹ́ ṣe fi hàn pé òun “fẹ́ kí gbogbo èèyàn ronú pìwà dà.” (2 Pét. 3:9) Àá tún rí àtúnṣe tá a ṣe nípa ọ̀nà tá a lè gbà múra tá a bá ń lọ sáwọn ìpàdé àti àpéjọ.
Wọ́n Fi Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Sẹ́wọ̀n Torí Ohun Tí Wọ́n Gbà Gbọ́—Ibì Kọ̀ọ̀kan
Àwọn ibi tí wọ́n ti fi àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sẹ́wọ̀n torí wọ́n ń ṣe ohun tí wọ́n gbà gbọ́, wọ́n sì ń lo ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn tí wọ́n ní. Wọ́n máa ń hùwà ìkà sí wọn lẹ́wọ̀n nígbà míì.

