Ohun Tá A Ní
Wàá rí onírúurú ìtẹ̀jáde tó dá lórí Bíbélì níbẹ̀. O tún lè ka àwọn ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ àti Jí! tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde àtàwọn ìtẹ̀jáde míì tó wà nísàlẹ̀ yìí lórí Íńtánẹ́ẹ̀tì tàbí kó o wà wọ́n jáde. Tẹ́tí sí àwọn ìtẹ̀jáde wa tá a ti kà sílẹ̀ lórí ẹ̀rọ lóríṣiríṣi èdè. Tún wo àwọn fídíò wa tàbí kó o wà wọ́n jáde lóríṣiríṣi èdè, títí kan èdè adití.

