Yorùbá
Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Ẹ̀mí Ni Kí Ìwọ Náà Máa Fi Wò Ó (Apá 2)
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/502016234/univ/art/502016234_univ_sqr_xl.jpg

KÍ NI BÍBÉLÌ FI KỌ́NI GAN-AN? (ÌWÉ ÌKẸ́KỌ̀Ọ́)

Ojú Tí Ọlọ́run Fi Ń Wo Ẹ̀mí Ni Kí Ìwọ Náà Máa Fi Wò Ó (Apá 2)

Orí kẹtàlá ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? ni ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ yìí dá lé.

Wo ohun tí Bíbélì sọ nípa àṣìlò ẹ̀jẹ̀ àti bí ọ̀nà kan ṣoṣo tó tọ́ láti lò ó ṣe lè gba ẹ̀mí wa là.