Yorùbá
Kí Ni Ọlọ́run Ní Lọ́kàn Tó Fi Dá Ilẹ̀ Ayé? (Apá 3)
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/502014341/univ/art/502014341_univ_sqr_xl.jpg

KÍ NI BÍBÉLÌ FI KỌ́NI?

Kí Ni Ọlọ́run Ní Lọ́kàn Tó Fi Dá Ilẹ̀ Ayé? (Apá 3)

Orí kẹta ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? ni ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ yìí dá lé.

Ọlọ́run máa lo Ìjọba rẹ̀ láti mú kí ayé yìí rí bó ṣe fẹ́, yóò sì fòpin sí gbogbo ìṣòro tó ń yọ aráyé lẹ́nu.