ÌGBÀGBỌ́ NÍNÚ ỌLỌ́RUN

Kíka Bíbélì àti Kíkẹ́kọ̀ọ́ Rẹ̀

Yorùbá
Kíka Bíbélì àti Kíkẹ́kọ̀ọ́ Rẹ̀
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/1011580/univ/art/1011580_univ_sqr_xl.jpg

Kíka Bíbélì àti Kíkẹ́kọ̀ọ́ Rẹ̀

Bíbélì Kíkà

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Ka Bíbélì?

Báwo lọ̀pọ̀ èèyàn ti ṣe jàǹfààní látinú kíka Bíbélì?

Ètò Kíka Bíbélì

Ìbáà jẹ́ ètò Bíbélì kíkà ojoojúmọ́ lò ń wá tàbí ti ọdọọdún tàbí èyí tó wà fẹ́ni tó ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́ máa ka Bíbélì, ètò Bíbélì kíkà yìí máa wúlò fún ẹ.

Bíbélì Kíkà: Ibo Ni Mo Ti Fẹ́ Bẹ̀rẹ̀?

Àwọn àbá márùn-ún tó máa jẹ́ kó o gbádùn kíka Bíbélì lọ́nà tó rọrùn.

Báwo Ni Bíbélì Ṣe Lè Ràn Mí Lọ́wọ́?​—Apá Kìíní: Wo Ohun Tó Wà Nínú Bíbélì

Tó bá ṣẹlẹ̀ pé o rí àpótí ìṣura ńlá kan, ó dájú pé ó máa wù ẹ́ láti mọ nǹkan tó wà nínú ẹ̀? Bíbélì ò yàtọ̀ sí àpótí ìṣura. Àwọn ìṣura ọgbọ́n tó pọ̀ gan-an tó sì wúlò ló wà nínú ẹ̀.

Báwo ni Bíbélì Ṣe Lè Ràn Mí Lọ́wọ́?​—Apá Kejì: Jẹ́ Kí Bíbélì Gbádùn Mọ́ Ẹ

Ohun márun-un tó máa jé kó o rí ara ẹ nínú Bíbélì kíkà rẹ.

Báwo Ni Bíbélì Ṣe Lè Ràn Mí Lọ́wọ́?—Apá 3: Túbọ̀ Jàǹfààní Púpọ̀ Bó o Ṣe Ń Ka Bíbélì

Ohun mẹ́rin tó o lè ṣe kó o lè túbọ̀ jàǹfààní púpọ̀ bó o ṣe ń ka Bíbélì.

Àwọn Ọ̀dọ́ Sọ̀rọ̀ Nípa Kíka Bíbélì

Ìwé kíkà kì í fìgbà gbogbo rọrùn, àmọ́ téèyàn bá ń ka Bíbélì, ó lérè. Àwọn ọ̀dọ́ mẹ́rin ṣàlàyé àǹfààní tí wọ́n ń rí bí wọ́n ṣe ń ka Bíbélì.

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?—Èyí Tó Gùn

Bíbélì ń ran ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù èèyàn kárí ayé lọ́wọ́ láti rí ìdáhùn sí àwọn ìbéèrè pàtàkì nípa ìgbésí ayé. Ṣé ìwọ náà á fẹ́ jẹ́ ọ̀kan lára wọn?

Ohun Tó Máa Ràn Ẹ́ Lọ́wọ́ Láti Lóye Bíbélì

Tó bá jẹ́ pé wọ́n kọ Bíbélì lọ́nà tá a máa gbà lóye rẹ̀, ṣé ó tún yẹn kẹ́nì kan ràn wá lọ́wọ́ ká tó lóye rẹ̀?

Ki Nidi To Fi Ye Ko O Kekoo Bibeli?

Nje o ti ronu ri pe, ‘Mi o ki i raye,’ tabi ‘Mi o feran ki n maa sadehun’?

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Lóye Bíbélì?

Ọ̀p gbà pé ọba ìwé ni Bíbélì láìmọ bí wọ́n ṣe lè jàǹfààní nínú rẹ̀.

Kí Ló Yẹ Kí O Ṣe Kó O Lè Lóye Bíbélì?

O lè lóye ọ̀rọ̀ pàtàkì tó wà nínú ẹ̀.

Ṣe Òótọ́ Ni Ọ̀rọ̀ Inú Bíbélì?

Tó bá jẹ́ pé Ọlọ́run ló ni Bíbélì, á jẹ́ pé kò sí ìwé míì tá a lè fi í wé.

Ohun Tá A Fi Ń Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì

Lo àwọn ohun tá a fi ń kẹ́kọ̀ọ́ láti kọ́ ohun tó wà nínú Bíbélì. Ó máa jẹ́ kó o gbádùn ìkẹ́kọ̀ọ́ náà, wàá sì rí ìdáhùn tó ń tẹ́ni lọ́rùn sí àwọn ìbéèrè ẹ.