ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI

Jèhófà Máa San Wá Lẹ́san Tá A Bá Jẹ́ Adúróṣinṣin sí I

Yorùbá
Jèhófà Máa San Wá Lẹ́san Tá A Bá Jẹ́ Adúróṣinṣin sí I
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202017327/univ/art/202017327_univ_sqr_xl.jpg

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | DÁNÍẸ́LÌ 1-3

Jèhófà Máa San Wá Lẹ́san Tá A Bá Jẹ́ Adúróṣinṣin sí I

Jèhófà Máa San Wá Lẹ́san Tá A Bá Jẹ́ Adúróṣinṣin sí I

Ìtàn àwọn Hébérù mẹ́ta yẹn ń fún wa níṣìírí láti jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà

3:16-20, 26-29

Kí ni àwọn ẹsẹ Ìwé Mímọ́ yìí fi hàn pé a gbọ́dọ̀ máa ṣe tá a bá fẹ́ jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà?