ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI

“Ọ̀dọ̀ Jèhófà Ni Ìrànlọ́wọ́ Mi Ti Wá”

Yorùbá
“Ọ̀dọ̀ Jèhófà Ni Ìrànlọ́wọ́ Mi Ti Wá”
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202016326/univ/art/202016326_univ_sqr_xl.jpg

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | SÁÀMÙ 120-134

“Ọ̀dọ̀ Jèhófà Ni Ìrànlọ́wọ́ Mi Ti Wá”

“Ọ̀dọ̀ Jèhófà Ni Ìrànlọ́wọ́ Mi Ti Wá”

Orin Ìgòkè làwọn èèyàn máa ń pe Sáàmù 120 sí 134. Ọ̀pọ̀ èèyàn ló gbà pé orin yìí làwọn ọmọ Ísírẹ́lì máa ń fìdùnnú kọ nígbà tí wọ́n bá ń gba orí àwọn òkè ńlá Júdà lọ sí Jerúsálẹ́mù láti lọ ṣe àwọn àjọyọ̀ ọdọọdún.

Jèhófà ń dáàbò bò wá bí . . .

121:3-8

  • olùṣọ́ àgùntàn tó wà lójúfò

  • òjìji tó ń dáàbò boni lọ́wọ́ oòrùn

  • jagunjagun tó jẹ́ arógunmásàá