ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Káwa Kristẹni Máa Sapá Láti Tẹ̀ Síwájú?

Yorùbá
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Káwa Kristẹni Máa Sapá Láti Tẹ̀ Síwájú?
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202022411/univ/art/202022411_univ_sqr_xl.jpg
mwb22 November ojú ìwé 6

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Káwa Kristẹni Máa Sapá Láti Tẹ̀ Síwájú?

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Káwa Kristẹni Máa Sapá Láti Tẹ̀ Síwájú?

Àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa máa ń sapá kí ọwọ́ wọn lè tẹ àwọn àfojúsùn kan nínú ìjọsìn Ọlọ́run. Bí àpẹẹrẹ, àwọn kan ń sapá kí wọ́n lè di aṣáájú-ọ̀nà, àwọn míì fẹ́ ṣiṣẹ́ ní Bẹ́tẹ́lì tàbí kí wọ́n bá àwọn tó ń kọ́ ilé ètò Ọlọ́run ṣiṣẹ́. Bákan náà, àwọn arákùnrin kan ń sapá kí wọ́n lè di alábòójútó nínú ìjọ. (1Ti 3:1) Ṣé ìyẹn wá túmọ̀ sí pé ó yẹ káwa Kristẹni máa lépa àtiwà nípò ńlá?

Ẹ WO FÍDÍÒ NÁÀ KÍ NÌDÍ TÓ FI YẸ KÁ MÁA SAPÁ LÁTI TẸ̀ SÍWÁJÚ? (1TI 3:1), KẸ́ Ẹ SÌ DÁHÙN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ YÌÍ:

Báwo làwọn ẹsẹ Bíbélì yìí ṣe jẹ́ ká rí ìdí mẹ́ta tó fi yẹ ká sapá láti tẹ̀ síwájú?