ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI

Ṣé Ò Ń Ṣiṣẹ́ Lórí Ohun Tí Ò Ń Kọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run?

Yorùbá
Ṣé Ò Ń Ṣiṣẹ́ Lórí Ohun Tí Ò Ń Kọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run?
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202023180/univ/art/202023180_univ_sqr_xl.jpg
mwb23 May ojú ìwé 12

Jòsáyà fa aṣọ ẹ̀ ya nígbà tó gbọ́ ohun tí ìwé òfin Jèhófà sọ

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Ṣé Ò Ń Ṣiṣẹ́ Lórí Ohun Tí Ò Ń Kọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run?

Ṣé Ò Ń Ṣiṣẹ́ Lórí Ohun Tí Ò Ń Kọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run?

Jòsáyà fara balẹ̀ tẹ́tí sí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run (2Kr 34:18, 19)

Ó ṣe gbogbo ohun tó lè ṣe kó lè lóye ohun tó gbọ́ nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run (2Kr 34:21; it-1 1157 ¶4; wo àwòrán iwájú ìwé)

Ó ṣiṣẹ́ lórí ohun tó gbọ́ (2Kr 34:33; w09 6/15 10 ¶20)

BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé mo máa ń tètè ṣiṣẹ́ lórí ohun tí mo kà nípa Jèhófà nínú Bíbélì Ọ̀rọ̀ rẹ̀?’