ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI

Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn

Yorùbá
Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202022176/univ/art/202022176_univ_sqr_xl.jpg
mwb22 May ojú ìwé 9

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn

Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn

Dáfídì wá ẹni tó lè fìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn sí nínú ilé Sọ́ọ̀lù (2Sa 9:1; w06 6/15 14 ¶6)

Dáfídì gbé ìgbésẹ̀ láti ran Mefibóṣétì lọ́wọ́ láìjáfara (1Sa 20:15, 42; 2Sa 9:5-7; w05 5/15 17 ¶12)

Dáfídì ní kí Síbà máa bójú tó ogún Mefibóṣétì (2Sa 9:9, 10; w02 2/15 14 ¶10)

Dáfídì ò gbàgbé ìlérí tó ṣe fún Jónátánì. Ó yẹ káwa náà máa fìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn sáwọn ará wa.​—Sm 41:1, 2; Owe 19:17.