ÌWÉ ÌPÀDÉ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI IṢẸ́ ÒJÍṢẸ́ ÀWA KRISTẸNI

Bẹ Jèhófà Pé Kó Fún Ẹ Ní Ìfaradà Kó sì Tù Ẹ́ Nínú

Yorùbá
Bẹ Jèhófà Pé Kó Fún Ẹ Ní Ìfaradà Kó sì Tù Ẹ́ Nínú
https://cms-imgp.jw-cdn.org/img/p/202019085/univ/art/202019085_univ_sqr_xl.jpg

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | RÓÒMÙ 15-16

Bẹ Jèhófà Pé Kó Fún Ẹ Ní Ìfaradà Kó sì Tù Ẹ́ Nínú

Bẹ Jèhófà Pé Kó Fún Ẹ Ní Ìfaradà Kó sì Tù Ẹ́ Nínú

15:4-7

Ọ̀kan lára àwọn nǹkan tí Jèhófà máa ń lò láti pèsè ìtùnú àti ìfaradà fún wa ni Bíbélì Ọ̀rọ̀ rẹ̀. Báwo ni àpẹẹrẹ àwọn tó wà nínú Bíbélì yìí ṣe fún ẹ ní ìṣírí àti ìtùnú?

  • Nóà

  • Jósẹ́fù

  • Dáfídì